Psalms 86:9-10
9
Gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè tí ìwọ dá
yóò wá, láti wá jọ́sìn níwájú rẹ,
Olúwa
;
wọn ó mú ògo wà fún orúkọ rẹ̀.
10
Nítorí pé ìwọ tóbi, ìwọ sì ń ṣe ohun ìyanu;
ìwọ nìkan ni Ọlọ́run.
Copyright information for
YorBMYO